Bí ènìyàn se lè jẹ́ ọmọ Orílẹ̀ èdè Nàìjíríà
25(1) O lè jẹ́ ọmọ bíbí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà nípasẹ̀ ibi tí: a) wọ́n bá bí ẹ ní Nàìjíríà síwájú ọjọ́ kiní oṣù kẹ̀wá ọdún 1960 tàbí tí bàbá, ìyá, tàbí ìyá bàbá, ìyá màmá, bàbá bàbá tàbí bàbá ìyá rẹ jẹ́ ọmọ ìlú kan ní Nàìjíríà. Ṣùgbọ́n, o kì yóò jẹ́ ọmọ orílẹ̀ èdè […]